^
2 Samuẹli
Dafidi gbọ́ ti ikú Saulu ọba
A yan Dafidi ní ọba Juda
Ogun láàrín ilé Dafidi àti Saulu
Abneri àti Iṣboṣeti jà
Abneri wá kí Dafidi ní Hebroni
Joabu gbọ́ nípa wíwá Abneri sí Hebroni
Joabu pa Abneri
Ikú Iṣboṣeti
A fi Dafidi jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli
Dafidi fi agbára gba Jerusalẹmu
Dafidi ṣẹ́gun àwọn Filistini
A gbé àpótí ẹ̀rí wá sí Jerusalẹmu
Ẹ̀ṣẹ̀ Mikali
Ìlérí Ọlọ́run si Dafidi
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kọ̀ fún Dafidi láti kọ́ tẹmpili
Àdúrà Dafidi
Dafidi ń ti ìṣẹ́gun dé ìṣẹ́gun
Àwọn ìránṣẹ́ Dafidi
Dafidi àti Mefiboṣeti
Dafidi ṣẹ́gun Ammoni
Àwọn ogun Siria àti Ammoni sá níwájú Israẹli
Ìṣẹ́gun lórí ogun Ammoni àti Siria ní Helami
Dafidi àti Batṣeba
Dafidi tan Uriah wá sílé
Dafidi pàṣẹ kí wọn ó pa Uriah ní ogun
Dafidi fẹ́ Batṣeba ní ìyàwó
Natani bá Dafidi wí
Ọmọ náà kú
Batṣeba sì tún bí ọmọ mìíràn tí a pè ní Solomoni
Ìṣẹ́gun Dafidi lórí àwọn Ammoni
Amnoni àti Tamari
Absalomu kọlu Amnoni
Absalomu sálọ sí Geṣuri
Absalomu padà si Jerusalẹmu
Ẹ̀bẹ̀ ní ti Absalomu
Dafidi mọ̀ pé Joabu ni ó ṣe èyí
Absalomu padà wá sí ilé
Ẹwà Absalomu àti àwọn ọmọ rẹ̀
Ọgbọ́n ẹ̀wẹ́ Absalomu
Absalomu dìtẹ̀ sí Dafidi baba rẹ̀
Dafidi sálọ kúrò lórí oyè
Ìwà òótọ́ Itai ará Gitti
A gbé àpótí ẹ̀rí padà sí ìlú Jerusalẹmu
Ahitofeli lọ́wọ́ sí ìdìtẹ̀ náà
Huṣai padà sí Jerusalẹmu
Dafidi àti Ṣiba
Ṣimei Bú Dafidi
Huṣai farahàn Absalomu bí ẹni tí ó ní ìfẹ́ sí i
Absalomu wọlé tọ àwọn obìnrin baba rẹ̀
Ahitofeli gbìmọ̀ pé kí a lépa Dafidi
Huṣai fi ọgbọ́n yí ìmọ̀ náà po
Huṣai ránṣẹ́ sí Dafidi nípa ìmọ̀ náà
Ahitofeli pokùnso
Wọ́n pàdé ogun ní igbó Efraimu
Joabu sì kọlu Absalomu
Dafidi ṣọ̀fọ̀
Joabu bá Dafidi wí gidigidi
Àwọn àgbà mú Dafidi ọba padà
Ọba dáríjì Ṣimei
Mefiboṣeti ṣe àlàyé fún Dafidi
Dafidi súre fún Barsillai
Israẹli ń jowú
Ṣeba ṣọ̀tẹ̀ sí Dafidi
Joabu fi idà gún Amasa, ó sì kú
Joabu lépa Seba
Wọ́n gé Ṣeba lórí
Àwọn ìránṣẹ́ Dafidi
Àwọn ará Gibeoni gba ẹ̀san
Síso Àwọn Ènìyàn Saulu Méje Rọ̀
Ìṣẹ́gun lórí Filistini
Orin ìyìn Dafidi
Ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi
Iṣẹ́ àwọn alágbára tí Dafidi ní
Kíka àwọn ènìyàn Israẹli
Dafidi yan ìbáwí Olúwa
Pẹpẹ ní ibi ìpakà Ornani