^
Gẹnẹsisi
Ìbẹ̀rẹ̀ dídá ayé
Adamu àti Efa
Ìṣubú ènìyàn
Kaini àti Abeli
Ìran Adamu títí dé ìran Noa
Ìkún omi
Noa àti ìkún omi
Ìkún omi gbẹ
Májẹ̀mú Ọlọ́run pẹ̀lú Noa
Àwọn ọmọ Noa
Ìran àwọn ọmọ Noa
Ìran Jafeti
Ìran Hamu
Ìran Ṣemu
Ilé ìṣọ́ Babeli
Ìran Ṣemu tó fi dé ti Abramu
Ìgbé ayé Abrahamu
Ìpè Abramu
Abramu ní Ejibiti
Ìpinyà Abramu àti Lọti
Abramu gba Lọti là
Májẹ̀mú Ọlọ́run pẹ̀lú Abramu
Hagari àti Iṣmaeli
Májẹ̀mú Ilà abẹ́ kíkọ
Àwọn àlejò mẹ́ta
Abrahamu bẹ Olúwa nítorí Sodomu
Ìparun Sodomu àti Gomorra
Lọti àti àwọn ọmọ rẹ̀ obìnrin
Abrahamu àti Abimeleki
Ìbí Isaaki
A lé Hagari àti Iṣmaeli jáde
Májẹ̀mú ní Beerṣeba
Ọlọ́run dán Abrahamu wò
Àwọn ọmọ Nahori
Ikú Sara
Isaaki àti Rebeka
Ikú Abrahamu
Àwọn ìran Iṣmaeli
Jakọbu25:18 Jakọbu yí ni a mọ̀ sí Israẹli. àti Esau
Isaaki àti Abimeleki
Isaaki súre fún Jakọbu
Jakọbu sálọ sí ọ̀dọ̀ Labani
Àlá Jakọbu ní Beteli
Jakọbu dé Padani-Aramu
Jakọbu fẹ́ àwọn ọmọ Labani Lea àti Rakeli
Àwọn ọmọ Jakọbu
Agbo ẹran Jakọbu pọ̀ sí i
Jakọbu sá kúrò lọ́dọ̀ Labani
Labani lépa Jakọbu
Jakọbu gbáradì láti pàdé Esau
Jakọbu bá Ọlọ́run ja ìjàkadì
Jakọbu àti Esau pàdé
Dina àti àwọn ará Ṣekemu
Jakọbu padà sí Beteli
Ikú Rakeli àti Isaaki
Àwọn ìránṣẹ́ Esau
Àwọn aláṣẹ Edomu
Àlá Josẹfu
Àwọn arákùnrin Josẹfu tà á
Juda àti Tamari
Josẹfu àti aya Potifari
Agbọ́tí àti alásè
Àwọn àlá Farao
Josẹfu di alábojútó ilẹ̀ Ejibiti
Àwọn arákùnrin Josẹfu lọ sí Ejibiti
Ìrìnàjò ẹ̀ẹ̀kejì lọ sí Ejibiti
Kọ́ọ̀bù idẹ nínú àpò
Josẹfu fi ara rẹ̀ hàn fún àwọn arákùnrin rẹ̀
Jakọbu lọ sí Ejibiti
Josẹfu àti ìyàn ní ilẹ̀ Ejibiti
Manase àti Efraimu
Ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Jakọbu sí àwọn ọmọ rẹ̀
Ikú Jakọbu
Josẹfu fi ọkàn àwọn arákùnrin rẹ̀ balẹ̀
Ikú Josẹfu